×

Eyin ahlul-kitab, dajudaju Ojise Wa ti de ba yin, ti o n 5:19 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah Al-Ma’idah ⮕ (5:19) ayat 19 in Yoruba

5:19 Surah Al-Ma’idah ayat 19 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah Al-Ma’idah ayat 19 - المَائدة - Page - Juz 6

﴿يَٰٓأَهۡلَ ٱلۡكِتَٰبِ قَدۡ جَآءَكُمۡ رَسُولُنَا يُبَيِّنُ لَكُمۡ عَلَىٰ فَتۡرَةٖ مِّنَ ٱلرُّسُلِ أَن تَقُولُواْ مَا جَآءَنَا مِنۢ بَشِيرٖ وَلَا نَذِيرٖۖ فَقَدۡ جَآءَكُم بَشِيرٞ وَنَذِيرٞۗ وَٱللَّهُ عَلَىٰ كُلِّ شَيۡءٖ قَدِيرٞ ﴾
[المَائدة: 19]

Eyin ahlul-kitab, dajudaju Ojise Wa ti de ba yin, ti o n se alaye (oro) fun yin leyin asiko ti A ti da awon Ojise duro, nitori ki e ma baa wi pe: “Ko si oniroo idunnu tabi olukilo kan ti o de ba wa.” Nitori naa, dajudaju oniroo idunnu ati olukilo kan ti de ba yin. Allahu si ni Alagbara lori gbogbo nnkan

❮ Previous Next ❯

ترجمة: ياأهل الكتاب قد جاءكم رسولنا يبين لكم على فترة من الرسل أن, باللغة اليوربا

﴿ياأهل الكتاب قد جاءكم رسولنا يبين لكم على فترة من الرسل أن﴾ [المَائدة: 19]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Ẹ̀yin ahlul-kitāb, dájúdájú Òjíṣẹ́ Wa ti dé ba yín, tí ó ń ṣe àlàyé (ọ̀rọ̀) fun yín lẹ́yìn àsìkò tí A ti dá àwọn Òjísẹ́ dúró, nítorí kí ẹ má baà wí pé: “Kò sí oníròó ìdùnnú tàbí olùkìlọ̀ kan tí ó dé bá wa.” Nítorí náà, dájúdájú oníròó ìdùnnú àti olùkìlọ̀ kan ti dé ba yín. Allāhu sì ni Alágbára lórí gbogbo n̄ǹkan
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek