×

(E ranti) nigba ti (Anabi) ’Ibrohim so pe: “Oluwa mi, se ilu 2:126 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah Al-Baqarah ⮕ (2:126) ayat 126 in Yoruba

2:126 Surah Al-Baqarah ayat 126 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah Al-Baqarah ayat 126 - البَقَرَة - Page - Juz 1

﴿وَإِذۡ قَالَ إِبۡرَٰهِـۧمُ رَبِّ ٱجۡعَلۡ هَٰذَا بَلَدًا ءَامِنٗا وَٱرۡزُقۡ أَهۡلَهُۥ مِنَ ٱلثَّمَرَٰتِ مَنۡ ءَامَنَ مِنۡهُم بِٱللَّهِ وَٱلۡيَوۡمِ ٱلۡأٓخِرِۚ قَالَ وَمَن كَفَرَ فَأُمَتِّعُهُۥ قَلِيلٗا ثُمَّ أَضۡطَرُّهُۥٓ إِلَىٰ عَذَابِ ٱلنَّارِۖ وَبِئۡسَ ٱلۡمَصِيرُ ﴾
[البَقَرَة: 126]

(E ranti) nigba ti (Anabi) ’Ibrohim so pe: “Oluwa mi, se ilu yii ni ilu ifayabale. Ki O si pese awon eso fun awon ara ibe (iyen) enikeni ninu won ti o ba ni igbagbo ododo ninu Allahu ati Ojo Ikeyin.” (Allahu) so pe: "Ati eni ti o ba sai gbagbo, Emi yoo fun un ni igbadun die. Leyin naa, Mo maa taari re sinu iya Ina. Ikangun naa si buru

❮ Previous Next ❯

ترجمة: وإذ قال إبراهيم رب اجعل هذا بلدا آمنا وارزق أهله من الثمرات, باللغة اليوربا

﴿وإذ قال إبراهيم رب اجعل هذا بلدا آمنا وارزق أهله من الثمرات﴾ [البَقَرَة: 126]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
(Ẹ rántí) nígbà tí (Ànábì) ’Ibrọ̄hīm sọ pé: “Olúwa mi, ṣe ìlú yìí ní ìlú ìfàyàbalẹ̀. Kí O sì pèsè àwọn èso fún àwọn ará ibẹ̀ (ìyẹn) ẹnikẹ́ni nínú wọn tí ó bá ní ìgbàgbọ́ òdodo nínú Allāhu àti Ọjọ́ Ìkẹyìn.” (Allāhu) sọ pé: "Àti ẹni tí ó bá ṣàì gbàgbọ́, Èmi yóò fún un ní ìgbádùn díẹ̀. Lẹ́yìn náà, Mo máa taari rẹ̀ sínú ìyà Iná. Ìkángun náà sì burú
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek