×

Ti o ba je pe dajudaju won lo at-Taorah ati al-’Injil ati 5:66 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah Al-Ma’idah ⮕ (5:66) ayat 66 in Yoruba

5:66 Surah Al-Ma’idah ayat 66 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah Al-Ma’idah ayat 66 - المَائدة - Page - Juz 6

﴿وَلَوۡ أَنَّهُمۡ أَقَامُواْ ٱلتَّوۡرَىٰةَ وَٱلۡإِنجِيلَ وَمَآ أُنزِلَ إِلَيۡهِم مِّن رَّبِّهِمۡ لَأَكَلُواْ مِن فَوۡقِهِمۡ وَمِن تَحۡتِ أَرۡجُلِهِمۚ مِّنۡهُمۡ أُمَّةٞ مُّقۡتَصِدَةٞۖ وَكَثِيرٞ مِّنۡهُمۡ سَآءَ مَا يَعۡمَلُونَ ﴾
[المَائدة: 66]

Ti o ba je pe dajudaju won lo at-Taorah ati al-’Injil ati ohun ti A sokale fun won lati odo Oluwa won (iyen, al-Ƙur’an), won iba maa je lati oke won ati lati isale ese won. Ijo kan n be ninu won t’o duro deede, (amo) ohun ti opolopo ninu won n se nise buru

❮ Previous Next ❯

ترجمة: ولو أنهم أقاموا التوراة والإنجيل وما أنـزل إليهم من ربهم لأكلوا من, باللغة اليوربا

﴿ولو أنهم أقاموا التوراة والإنجيل وما أنـزل إليهم من ربهم لأكلوا من﴾ [المَائدة: 66]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Tí ó bá jẹ́ pé dájúdájú wọ́n lo at-Taorāh àti al-’Injīl àti ohun tí A sọ̀kalẹ̀ fún wọn láti ọ̀dọ̀ Olúwa wọn (ìyẹn, al-Ƙur’ān), wọn ìbá máa jẹ láti òkè wọn àti láti ìsàlẹ̀ ẹsẹ̀ wọn. Ìjọ kan ń bẹ nínú wọn t’ó dúró déédé, (àmọ́) ohun tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú wọn ń ṣe níṣẹ́ burú
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek