×

(Ranti) nigba ti (Anabi) Musa so fun ijo re pe e ranti 14:6 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah Ibrahim ⮕ (14:6) ayat 6 in Yoruba

14:6 Surah Ibrahim ayat 6 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah Ibrahim ayat 6 - إبراهِيم - Page - Juz 13

﴿وَإِذۡ قَالَ مُوسَىٰ لِقَوۡمِهِ ٱذۡكُرُواْ نِعۡمَةَ ٱللَّهِ عَلَيۡكُمۡ إِذۡ أَنجَىٰكُم مِّنۡ ءَالِ فِرۡعَوۡنَ يَسُومُونَكُمۡ سُوٓءَ ٱلۡعَذَابِ وَيُذَبِّحُونَ أَبۡنَآءَكُمۡ وَيَسۡتَحۡيُونَ نِسَآءَكُمۡۚ وَفِي ذَٰلِكُم بَلَآءٞ مِّن رَّبِّكُمۡ عَظِيمٞ ﴾
[إبراهِيم: 6]

(Ranti) nigba ti (Anabi) Musa so fun ijo re pe e ranti ike Allahu lori yin nigba ti O gba yin la lowo awon eniyan Fir‘aon, ti won n fi iya buruku je yin; won n dunnbu awon omokunrin yin, won si n da awon omobinrin yin si. Adanwo nla wa ninu iyen lati odo Oluwa yin

❮ Previous Next ❯

ترجمة: وإذ قال موسى لقومه اذكروا نعمة الله عليكم إذ أنجاكم من آل, باللغة اليوربا

﴿وإذ قال موسى لقومه اذكروا نعمة الله عليكم إذ أنجاكم من آل﴾ [إبراهِيم: 6]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
(Rántí) nígbà tí (Ànábì) Mūsā sọ fún ìjọ rẹ̀ pé ẹ rántí ìkẹ́ Allāhu lórí yín nígbà tí Ó gbà yín là lọ́wọ́ àwọn ènìyàn Fir‘aon, tí wọ́n ń fi ìyà burúkú jẹ yín; wọ́n ń dúnńbú àwọn ọmọkùnrin yín, wọ́n sì ń dá àwọn ọmọbìnrin yín sí. Àdánwò ńlá wà nínú ìyẹn láti ọ̀dọ̀ Olúwa yín
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek