×

(E ranti Anabi) Zakariyya nigba ti o pe Oluwa re pe: “Oluwa 21:89 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah Al-Anbiya’ ⮕ (21:89) ayat 89 in Yoruba

21:89 Surah Al-Anbiya’ ayat 89 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah Al-Anbiya’ ayat 89 - الأنبيَاء - Page - Juz 17

﴿وَزَكَرِيَّآ إِذۡ نَادَىٰ رَبَّهُۥ رَبِّ لَا تَذَرۡنِي فَرۡدٗا وَأَنتَ خَيۡرُ ٱلۡوَٰرِثِينَ ﴾
[الأنبيَاء: 89]

(E ranti Anabi) Zakariyya nigba ti o pe Oluwa re pe: “Oluwa mi, ma fi mi sile ni emi nikan (ti ko nii bimo). Iwo si loore julo ninu awon olujogun.”

❮ Previous Next ❯

ترجمة: وزكريا إذ نادى ربه رب لا تذرني فردا وأنت خير الوارثين, باللغة اليوربا

﴿وزكريا إذ نادى ربه رب لا تذرني فردا وأنت خير الوارثين﴾ [الأنبيَاء: 89]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
(Ẹ rántí Ànábì) Zakariyyā nígbà tí ó pe Olúwa rẹ̀ pé: “Olúwa mi, má fi mí sílẹ̀ ní èmi nìkan (tí kò níí bímọ). Ìwọ sì lóore jùlọ nínú àwọn olùjogún.”
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek