×

(Anabi) Muhammad ki i se baba eni kan kan ninu awon okunrin 33:40 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah Al-Ahzab ⮕ (33:40) ayat 40 in Yoruba

33:40 Surah Al-Ahzab ayat 40 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah Al-Ahzab ayat 40 - الأحزَاب - Page - Juz 22

﴿مَّا كَانَ مُحَمَّدٌ أَبَآ أَحَدٖ مِّن رِّجَالِكُمۡ وَلَٰكِن رَّسُولَ ٱللَّهِ وَخَاتَمَ ٱلنَّبِيِّـۧنَۗ وَكَانَ ٱللَّهُ بِكُلِّ شَيۡءٍ عَلِيمٗا ﴾
[الأحزَاب: 40]

(Anabi) Muhammad ki i se baba eni kan kan ninu awon okunrin yin, sugbon (o je) Ojise Allahu ati opin awon Anabi. Allahu si n je Onimo nipa gbogbo nnkan. opuro asookun sesin wule ni oun. Iro enu re ti po ju. Alagbari ponnbele si ni pelu. Iru ise aburu ti seeu Ahmada Tijani se fun ’Islam gele naa ni mirza ghulam Ahmad se. Awon mejeeji ni Poolu laaarin awa musulumi. E wo die ninu iro nla re. Mirza ghulam Ahmad so pe: ""Allahu so fun mi ni ede Larubawa pe bi omo Mi lo se wa si Mi."" (Tadhkirah “Ti o ba je pe Anabi Muhammad (sollalahu 'alayhi wa sallam) ni opin awon Anabi Olohun ko ye fun Anabi ‘Isa omo Moryam ('alaehi-ssolatu wa-ssalam) lati pada wa saye mo lopin aye.” Won tun so pe Anabi Muhammad (sollalahu 'alayhi wa sallam) ni opin awon Anabi Olohun amo isoro tiwon ni pe

❮ Previous Next ❯

ترجمة: ما كان محمد أبا أحد من رجالكم ولكن رسول الله وخاتم النبيين, باللغة اليوربا

﴿ما كان محمد أبا أحد من رجالكم ولكن رسول الله وخاتم النبيين﴾ [الأحزَاب: 40]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
(Ànábì) Muhammad kì í ṣe bàbá ẹnì kan kan nínú àwọn ọkùnrin yín, ṣùgbọ́n (ó jẹ́) Òjíṣẹ́ Allāhu àti òpin àwọn Ànábì. Allāhu sì ń jẹ́ Onímọ̀ nípa gbogbo n̄ǹkan. òpùrọ́ asòòkùn sẹ́sìn wulẹ̀ ni òun. Irọ́ ẹnu rẹ̀ ti pọ̀ jù. Alágbárí pọ́nńbélé sì ni pẹ̀lú. Irú iṣẹ́ aburú tí ṣeeu Ahmada Tijāni ṣe fún ’Islām gẹ́lẹ́ náà ni mirza ghulam Ahmad ṣe. Àwọn méjèèjì ni Pọ́ọ̀lù láààrin àwa mùsùlùmí. Ẹ wo díẹ̀ nínú irọ́ ńlá rẹ̀. Mirza ghulam Ahmad sọ pé: ""Allāhu sọ fún mi ní èdè Lárúbáwá pé bí ọmọ Mi ló ṣe wà sí Mi."" (Tadhkirah “Tí ó bá jẹ́ pé Ànábì Muhammad (sollalāhu 'alayhi wa sallam) ni òpin àwọn Ànábì Ọlọ́hun kò yẹ fún Ànábì ‘Īsā ọmọ Mọryam ('alaehi-ssọlātu wa-ssalām) láti padà wá sáyé mọ́ lópin ayé.” Wọ́n tún sọ pé Ànábì Muhammad (sollalāhu 'alayhi wa sallam) ni òpin àwọn Ànábì Ọlọ́hun àmọ́ ìṣòro tiwọn ni pé
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek