×

Dajudaju awon t’o so pe: "Allahu ni Oluwa wa." leyin naa, ti 41:30 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah Fussilat ⮕ (41:30) ayat 30 in Yoruba

41:30 Surah Fussilat ayat 30 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah Fussilat ayat 30 - فُصِّلَت - Page - Juz 24

﴿إِنَّ ٱلَّذِينَ قَالُواْ رَبُّنَا ٱللَّهُ ثُمَّ ٱسۡتَقَٰمُواْ تَتَنَزَّلُ عَلَيۡهِمُ ٱلۡمَلَٰٓئِكَةُ أَلَّا تَخَافُواْ وَلَا تَحۡزَنُواْ وَأَبۡشِرُواْ بِٱلۡجَنَّةِ ٱلَّتِي كُنتُمۡ تُوعَدُونَ ﴾
[فُصِّلَت: 30]

Dajudaju awon t’o so pe: "Allahu ni Oluwa wa." leyin naa, ti won duro sinsin, awon molaika yoo maa sokale wa ba won (ni ojo iku won, won si maa so pe: “E ma se paya, e ma se banuje. Ki e si dunnu si Ogba Idera eyi ti Won n se ni adehun fun yin)

❮ Previous Next ❯

ترجمة: إن الذين قالوا ربنا الله ثم استقاموا تتنـزل عليهم الملائكة ألا تخافوا, باللغة اليوربا

﴿إن الذين قالوا ربنا الله ثم استقاموا تتنـزل عليهم الملائكة ألا تخافوا﴾ [فُصِّلَت: 30]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Dájúdájú àwọn t’ó sọ pé: "Allāhu ni Olúwa wa." lẹ́yìn náà, tí wọ́n dúró ṣinṣin, àwọn mọlāika yóò máa sọ̀kalẹ̀ wá bá wọn (ní ọjọ́ ikú wọn, wọ́n sì máa sọ pé: “Ẹ má ṣe páyà, ẹ má ṣe banújẹ́. Kí ẹ sì dunnú sí Ọgbà Ìdẹ̀ra èyí tí Wọ́n ń ṣe ní àdéhùn fun yín)
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek