×

(Ranti) nigba ti Oluwa re gba adehun lowo awon omo Adam, O 7:172 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah Al-A‘raf ⮕ (7:172) ayat 172 in Yoruba

7:172 Surah Al-A‘raf ayat 172 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah Al-A‘raf ayat 172 - الأعرَاف - Page - Juz 9

﴿وَإِذۡ أَخَذَ رَبُّكَ مِنۢ بَنِيٓ ءَادَمَ مِن ظُهُورِهِمۡ ذُرِّيَّتَهُمۡ وَأَشۡهَدَهُمۡ عَلَىٰٓ أَنفُسِهِمۡ أَلَسۡتُ بِرَبِّكُمۡۖ قَالُواْ بَلَىٰ شَهِدۡنَآۚ أَن تَقُولُواْ يَوۡمَ ٱلۡقِيَٰمَةِ إِنَّا كُنَّا عَنۡ هَٰذَا غَٰفِلِينَ ﴾
[الأعرَاف: 172]

(Ranti) nigba ti Oluwa re gba adehun lowo awon omo Adam, O fa aromodomo won jade lati (ibadi ni) eyin (baba nla) won, O si fi won se elerii lori ara won pe: “Se Emi ko ni Oluwa yin ni?” Won so pe: “Rara – (Iwo ni Oluwa wa) - a jerii si i.” Nitori ki e ma baa so ni Ojo Ajinde pe: "Dajudaju awa je alaimo nipa eyi

❮ Previous Next ❯

ترجمة: وإذ أخذ ربك من بني آدم من ظهورهم ذريتهم وأشهدهم على أنفسهم, باللغة اليوربا

﴿وإذ أخذ ربك من بني آدم من ظهورهم ذريتهم وأشهدهم على أنفسهم﴾ [الأعرَاف: 172]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
(Rántí) nígbà tí Olúwa rẹ gba àdéhùn lọ́wọ́ àwọn ọmọ Ādam, Ó fa àrọ́mọdọ́mọ wọn jáde láti (ìbàdí ní) ẹ̀yìn (bàbá ńlá) wọn, Ó sì fi wọ́n ṣe ẹlẹ́rìí lórí ara wọn pé: “Ṣé Èmi kọ́ ni Olúwa yín ni?” Wọ́n sọ pé: “Rárá – (Ìwọ ni Olúwa wa) - a jẹ́rìí sí i.” Nítorí kí ẹ má baà sọ ní Ọjọ́ Àjíǹdé pé: "Dájúdájú àwa jẹ́ aláìmọ̀ nípa èyí
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek