×

Ati pe enikeni ninu won ti o ba wi pe: “Dajudaju emi 21:29 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah Al-Anbiya’ ⮕ (21:29) ayat 29 in Yoruba

21:29 Surah Al-Anbiya’ ayat 29 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah Al-Anbiya’ ayat 29 - الأنبيَاء - Page - Juz 17

﴿۞ وَمَن يَقُلۡ مِنۡهُمۡ إِنِّيٓ إِلَٰهٞ مِّن دُونِهِۦ فَذَٰلِكَ نَجۡزِيهِ جَهَنَّمَۚ كَذَٰلِكَ نَجۡزِي ٱلظَّٰلِمِينَ ﴾
[الأنبيَاء: 29]

Ati pe enikeni ninu won ti o ba wi pe: “Dajudaju emi ni olohun leyin Re.” Nitori iyen si ni A oo fi san an ni esan ina Jahanamo. Bayen si ni A se n san awon alabosi ni esan

❮ Previous Next ❯

ترجمة: ومن يقل منهم إني إله من دونه فذلك نجزيه جهنم كذلك نجزي, باللغة اليوربا

﴿ومن يقل منهم إني إله من دونه فذلك نجزيه جهنم كذلك نجزي﴾ [الأنبيَاء: 29]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Àti pé ẹnikẹ́ni nínú wọn tí ó bá wí pé: “Dájúdájú èmi ni ọlọ́hun lẹ́yìn Rẹ̀.” Nítorí ìyẹn sì ni A óò fi san án ní ẹ̀san iná Jahanamọ. Báyẹn sì ni A ṣe ń san àwọn alábòsí ní ẹ̀san
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek