×

Eyin ti A fun ni tira, e gbagbo ninu ohun ti A 4:47 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah An-Nisa’ ⮕ (4:47) ayat 47 in Yoruba

4:47 Surah An-Nisa’ ayat 47 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah An-Nisa’ ayat 47 - النِّسَاء - Page - Juz 5

﴿يَٰٓأَيُّهَا ٱلَّذِينَ أُوتُواْ ٱلۡكِتَٰبَ ءَامِنُواْ بِمَا نَزَّلۡنَا مُصَدِّقٗا لِّمَا مَعَكُم مِّن قَبۡلِ أَن نَّطۡمِسَ وُجُوهٗا فَنَرُدَّهَا عَلَىٰٓ أَدۡبَارِهَآ أَوۡ نَلۡعَنَهُمۡ كَمَا لَعَنَّآ أَصۡحَٰبَ ٱلسَّبۡتِۚ وَكَانَ أَمۡرُ ٱللَّهِ مَفۡعُولًا ﴾
[النِّسَاء: 47]

Eyin ti A fun ni tira, e gbagbo ninu ohun ti A sokale, ti o n fi ohun t’o je ododo rinle nipa eyi t’o wa pelu yin, siwaju ki A to fo awon oju kan, A si maa da a pada si (ipako) leyin won, tabi ki A sebi le won gege bi A se sebi le ijo Sabt. Ati pe ase Allahu maa se

❮ Previous Next ❯

ترجمة: ياأيها الذين أوتوا الكتاب آمنوا بما نـزلنا مصدقا لما معكم من قبل, باللغة اليوربا

﴿ياأيها الذين أوتوا الكتاب آمنوا بما نـزلنا مصدقا لما معكم من قبل﴾ [النِّسَاء: 47]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Ẹ̀yin tí A fún ní tírà, ẹ gbàgbọ́ nínú ohun tí A sọ̀kalẹ̀, tí ó ń fi ohun t’ó jẹ́ òdodo rinlẹ̀ nípa èyí t’ó wà pẹ̀lú yín, ṣíwájú kí Á tó fọ́ àwọn ojú kan, A sì máa dá a padà sí (ìpàkọ́) lẹ́yìn wọn, tàbí kí Á ṣẹ́bi lé wọn gẹ́gẹ́ bí A ṣe ṣẹ́bi lé ìjọ Sabt. Àti pé àṣẹ Allāhu máa ṣẹ
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek