×

Won so pe: “Won ni wa larasiwaju ki o to wa ba 7:129 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah Al-A‘raf ⮕ (7:129) ayat 129 in Yoruba

7:129 Surah Al-A‘raf ayat 129 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah Al-A‘raf ayat 129 - الأعرَاف - Page - Juz 9

﴿قَالُوٓاْ أُوذِينَا مِن قَبۡلِ أَن تَأۡتِيَنَا وَمِنۢ بَعۡدِ مَا جِئۡتَنَاۚ قَالَ عَسَىٰ رَبُّكُمۡ أَن يُهۡلِكَ عَدُوَّكُمۡ وَيَسۡتَخۡلِفَكُمۡ فِي ٱلۡأَرۡضِ فَيَنظُرَ كَيۡفَ تَعۡمَلُونَ ﴾
[الأعرَاف: 129]

Won so pe: “Won ni wa larasiwaju ki o to wa ba wa ati leyin ti o de ba wa.” (Anabi Musa) so pe: “O le je pe Allahu yoo pa awon ota yin run. O si maa fi yin ropo (won) lori ile. Nigba naa, (Allahu) yo si wo bi eyin naa yoo se maa se.”

❮ Previous Next ❯

ترجمة: قالوا أوذينا من قبل أن تأتينا ومن بعد ما جئتنا قال عسى, باللغة اليوربا

﴿قالوا أوذينا من قبل أن تأتينا ومن بعد ما جئتنا قال عسى﴾ [الأعرَاف: 129]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Wọ́n sọ pé: “Wọ́n ni wá láraṣíwájú kí o tó wá bá wa àti lẹ́yìn tí o dé bá wa.” (Ànábì Mūsā) sọ pé: “Ó lè jẹ́ pé Allāhu yóò pa àwọn ọ̀tá yín run. Ó sì máa fi yín rọ́pò (wọn) lórí ilẹ̀. Nígbà náà, (Allāhu) yó sì wo bí ẹ̀yin náà yóò ṣe máa ṣe.”
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek