×

Dajudaju awon t’o sai gbagbo, won n na dukia won nitori ki 8:36 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah Al-Anfal ⮕ (8:36) ayat 36 in Yoruba

8:36 Surah Al-Anfal ayat 36 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah Al-Anfal ayat 36 - الأنفَال - Page - Juz 9

﴿إِنَّ ٱلَّذِينَ كَفَرُواْ يُنفِقُونَ أَمۡوَٰلَهُمۡ لِيَصُدُّواْ عَن سَبِيلِ ٱللَّهِۚ فَسَيُنفِقُونَهَا ثُمَّ تَكُونُ عَلَيۡهِمۡ حَسۡرَةٗ ثُمَّ يُغۡلَبُونَۗ وَٱلَّذِينَ كَفَرُوٓاْ إِلَىٰ جَهَنَّمَ يُحۡشَرُونَ ﴾
[الأنفَال: 36]

Dajudaju awon t’o sai gbagbo, won n na dukia won nitori ki won le seri awon eniyan kuro loju ona (esin) Allahu. Won si n na a lo (bee). Leyin naa, o maa di abamo fun won. Leyin naa, A si maa bori won. Ati pe awon t’o sai gbagbo, inu ina Jahanamo ni A maa ko won jo si

❮ Previous Next ❯

ترجمة: إن الذين كفروا ينفقون أموالهم ليصدوا عن سبيل الله فسينفقونها ثم تكون, باللغة اليوربا

﴿إن الذين كفروا ينفقون أموالهم ليصدوا عن سبيل الله فسينفقونها ثم تكون﴾ [الأنفَال: 36]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Dájúdájú àwọn t’ó ṣàì gbàgbọ́, wọ́n ń ná dúkìá wọn nítorí kí wọ́n lè ṣẹ́rí àwọn ènìyàn kúrò lójú ọ̀nà (ẹ̀sìn) Allāhu. Wọ́n sì ń ná a lọ (bẹ́ẹ̀). Lẹ́yìn náà, ó máa di àbámọ̀ fún wọn. Lẹ́yìn náà, A sì máa borí wọn. Àti pé àwọn t’ó ṣàì gbàgbọ́, inú iná Jahanamọ ni A máa kó wọn jọ sí
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek