×

Leyin naa, dajudaju Oluwa re - nipa awon t’o gbe ilu won 16:110 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah An-Nahl ⮕ (16:110) ayat 110 in Yoruba

16:110 Surah An-Nahl ayat 110 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah An-Nahl ayat 110 - النَّحل - Page - Juz 14

﴿ثُمَّ إِنَّ رَبَّكَ لِلَّذِينَ هَاجَرُواْ مِنۢ بَعۡدِ مَا فُتِنُواْ ثُمَّ جَٰهَدُواْ وَصَبَرُوٓاْ إِنَّ رَبَّكَ مِنۢ بَعۡدِهَا لَغَفُورٞ رَّحِيمٞ ﴾
[النَّحل: 110]

Leyin naa, dajudaju Oluwa re - nipa awon t’o gbe ilu won ju sile leyin ti awon alaigbagbo ti ko ifooro ba won, leyin naa, ti won jagun esin, ti won si se suuru - dajudaju Oluwa re ni Alaforijin, Asake-orun (fun won) leyin (ifooro ti won ri lodo awon alaigbagbo)

❮ Previous Next ❯

ترجمة: ثم إن ربك للذين هاجروا من بعد ما فتنوا ثم جاهدوا وصبروا, باللغة اليوربا

﴿ثم إن ربك للذين هاجروا من بعد ما فتنوا ثم جاهدوا وصبروا﴾ [النَّحل: 110]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Lẹ́yìn náà, dájúdájú Olúwa rẹ - nípa àwọn t’ó gbé ìlú wọn jù sílẹ̀ lẹ́yìn tí àwọn aláìgbàgbọ́ ti kó ìfòòró bá wọn, lẹ́yìn náà, tí wọ́n jagun ẹ̀sìn, tí wọ́n sì ṣe sùúrù - dájúdájú Olúwa rẹ ni Aláforíjìn, Àṣàkẹ́-ọ̀run (fún wọn) lẹ́yìn (ìfòòró tí wọ́n rí lọ́dọ̀ àwọn aláìgbàgbọ́)
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek