×

Awon ami t’o yanju wa ninu re; ibuduro (Anabi) ’Ibrohim. Enikeni ti 3:97 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah al-‘Imran ⮕ (3:97) ayat 97 in Yoruba

3:97 Surah al-‘Imran ayat 97 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah al-‘Imran ayat 97 - آل عِمران - Page - Juz 4

﴿فِيهِ ءَايَٰتُۢ بَيِّنَٰتٞ مَّقَامُ إِبۡرَٰهِيمَۖ وَمَن دَخَلَهُۥ كَانَ ءَامِنٗاۗ وَلِلَّهِ عَلَى ٱلنَّاسِ حِجُّ ٱلۡبَيۡتِ مَنِ ٱسۡتَطَاعَ إِلَيۡهِ سَبِيلٗاۚ وَمَن كَفَرَ فَإِنَّ ٱللَّهَ غَنِيٌّ عَنِ ٱلۡعَٰلَمِينَ ﴾
[آل عِمران: 97]

Awon ami t’o yanju wa ninu re; ibuduro (Anabi) ’Ibrohim. Enikeni ti o ba wo inu re ti di eni ifayabale. Allahu se abewo si Ile naa ni dandan fun awon eniyan, t’o lagbara ona ti o maa gba debe. Enikeni ti o ba si sai gbagbo,dajudaju Allahu ni Oloro ti ko bukata si gbogbo eda

❮ Previous Next ❯

ترجمة: فيه آيات بينات مقام إبراهيم ومن دخله كان آمنا ولله على الناس, باللغة اليوربا

﴿فيه آيات بينات مقام إبراهيم ومن دخله كان آمنا ولله على الناس﴾ [آل عِمران: 97]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Àwọn àmì t’ó yanjú wà nínú rẹ̀; ibùdúró (Ànábì) ’Ibrọ̄hīm. Ẹnikẹ́ni tí ó bá wọ inú rẹ̀ ti di ẹni ìfàyàbalẹ̀. Allāhu ṣe àbẹ̀wò sí Ilé náà ní dandan fún àwọn ènìyàn, t’ó lágbára ọ̀nà tí ó máa gbà débẹ̀. Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì ṣàì gbàgbọ́,dájúdájú Allāhu ni Ọlọ́rọ̀ tí kò bùkátà sí gbogbo ẹ̀dá
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek