×

Iwo ko l’o maa fi ona mo awon afoju nibi isina won. 30:53 Yoruba translation

Quran infoYorubaSurah Ar-Rum ⮕ (30:53) ayat 53 in Yoruba

30:53 Surah Ar-Rum ayat 53 in Yoruba (اليوربا)

Quran with Yoruba translation - Surah Ar-Rum ayat 53 - الرُّوم - Page - Juz 21

﴿وَمَآ أَنتَ بِهَٰدِ ٱلۡعُمۡيِ عَن ضَلَٰلَتِهِمۡۖ إِن تُسۡمِعُ إِلَّا مَن يُؤۡمِنُ بِـَٔايَٰتِنَا فَهُم مُّسۡلِمُونَ ﴾
[الرُّوم: 53]

Iwo ko l’o maa fi ona mo awon afoju nibi isina won. Ko si eni ti o maa mu gbo oro afi eni ti o ba gba awon ayah Wa gbo. Awon si ni (musulumi) olujupa-juse-sile fun Allahu. Allahu (subhanahu wa ta'ala) l’O n sise iyanu. Ko si si Anabi tabi Ojise Olohun kan ti Allahu ko fun ni ise iyanu kan tabi omiran se ni ibamu si igba eni kookan won. Bee si ni eyikeyii ise iyanu ti o ba towo Anabi tabi Ojise kan waye ko so Anabi tabi Ojise naa di oluwa ati olugbala. Allahu nikan soso ni Oluwa ati Olugbala aye ati orun. Nitori naa fun alekun lori awon ise iyanu Anabi ‘Isa omo Moryam ('alaehi-ssolatu wa-ssalam) ti Allahu ba fe. Allahu si ni Alagbara lori gbogbo nnkan. Amo awon kristieni gege bi isesi won bi o se n wu u to ati bi o se n jerankan to ni pe ki gbogbo awon eniyan re gbagbo ninu Allahu. Amo won ko gbagbo

❮ Previous Next ❯

ترجمة: وما أنت بهاد العمي عن ضلالتهم إن تسمع إلا من يؤمن بآياتنا, باللغة اليوربا

﴿وما أنت بهاد العمي عن ضلالتهم إن تسمع إلا من يؤمن بآياتنا﴾ [الرُّوم: 53]

Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Ìwọ kọ́ l’o máa fi ọ̀nà mọ àwọn afọ́jú níbi ìṣìnà wọn. Kò sí ẹni tí o máa mú gbọ́ ọ̀rọ̀ àfi ẹni tí ó bá gba àwọn āyah Wa gbọ́. Àwọn sì ni (mùsùlùmí) olùjupá-jusẹ̀-sílẹ̀ fún Allāhu. Allāhu (subhānahu wa ta'ālā) l’Ó ń ṣiṣẹ́ ìyanu. Kò sì sí Ànábì tàbí Òjíṣẹ́ Ọlọ́hun kan tí Allāhu kò fún ní iṣẹ́ ìyanu kan tàbí òmíràn ṣe ní ìbámu sí ìgbà ẹnì kọ̀ọ̀kan wọn. Bẹ́ẹ̀ sì ni èyíkéyìí iṣẹ́ ìyanu tí ó bá tọwọ́ Ànábì tàbí Òjíṣẹ́ kan wáyé kò sọ Ànábì tàbí Òjíṣẹ́ náà di olúwa àti olùgbàlà. Allāhu nìkan ṣoṣo ní Olúwa àti Olùgbàlà ayé àti ọ̀run. Nítorí náà fún àlékún lórí àwọn iṣẹ́ ìyanu Ànábì ‘Īsā ọmọ Mọryam ('alaehi-ssọlātu wa-ssalām) tí Allāhu bá fẹ́. Allāhu sì ni Alágbára lórí gbogbo n̄ǹkan. Àmọ́ àwọn kristiẹni gẹ́gẹ́ bí ìṣesí wọn bí ó ṣe ń wù ú tó àti bí ó ṣe ń jẹ̀rankàn tó ni pé kí gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀ gbàgbọ́ nínú Allāhu. Àmọ́ wọn kò gbàgbọ́
❮ Previous Next ❯

Verse in more languages

Transliteration Bangla Bosnian German English Persian French Hindi Indonesian Kazakh Dutch Russian Spanish Turkish Urdu Uzbek